Yorùbá Bibeli

2. A. Ọba 13:6 Yorùbá Bibeli (YCE)

Ṣugbọn nwọn kò lọ kuro ninu ẹ̀ṣẹ ile Jeroboamu, ẹniti o mu Israeli ṣẹ̀, ṣugbọn nwọn rìn ninu rẹ̀: ere-oriṣa si wà ni Samaria pẹlu.

2. A. Ọba 13

2. A. Ọba 13:4-12