Yorùbá Bibeli

2. A. Ọba 10:31 Yorùbá Bibeli (YCE)

Ṣugbọn Jehu kò ṣe akiyesi lati ma fi gbogbo ọkàn rẹ̀ rin ninu ofin Oluwa Ọlọrun Israeli: nitoriti kò yà kuro ninu ẹ̀ṣẹ Jeroboamu, ti o mu Israeli ṣẹ̀.

2. A. Ọba 10

2. A. Ọba 10:26-36