Yorùbá Bibeli

2. A. Ọba 10:29 Yorùbá Bibeli (YCE)

Ṣugbọn Jehu kò kuro ninu ẹ̀ṣẹ Jeroboamu ọmọ Nebati, ti o mu Israeli ṣẹ̀, eyinì ni, awọn ẹgbọ̀rọ malu wura ti o wà ni Beteli, ati eyiti o wà ni Dani.

2. A. Ọba 10

2. A. Ọba 10:24-32