Yorùbá Bibeli

2. Kor 5:1 Yorùbá Bibeli (YCE)

NITORI awa mọ̀ pe, bi ile agọ́ wa ti aiye bá wó, awa ni ile kan lati ọdọ Ọlọrun, ile ti a kò fi ọwọ́ kọ́, ti aiyeraiye ninu awọn ọrun.

2. Kor 5

2. Kor 5:1-9