Yorùbá Bibeli

Esr 10:29-38 Yorùbá Bibeli (YCE)

29. Ati ninu awọn ọmọ Bani; Meṣullamu, Malluki, ati Adaiah, Jaṣubu, ati Ṣeali ati Ramoti.

30. Ati ninu awọn ọmọ Pahat-moabu Adma ati Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleeli, ati Binnui, ati Manasse.

31. Ati ninu awọn ọmọ Harimu; Elieseri, Isṣjah, Malkiah, Ṣemaiah, Ṣimeoni,

32. Benjamini, Malluki, ati Ṣemariah.

33. Ninu awọn ọmọ Haṣumu; Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifeleti, Jeremai, Manasse, ati Ṣimei.

34. Ninu awọn ọmọ Bani; Maadai, Amramu ati Ueli.

35. Benaiah, Bedeiah, Kellu,

36. Faniah, Meremoti, Eliaṣibu,

37. Mattaniah, Mattenai ati Jaasau,

38. Ati Bani, ati Binnui, Ṣimei.