Yorùbá Bibeli

Esr 10:26-44 Yorùbá Bibeli (YCE)

26. Ati ninu awọn ọmọ Elamu; Mattaniah, Sekariah, ati Jehieli, ati Abdi, ati Jeremoti, ati Elijah.

27. Ati ninu awọn ọmọ Sattu; Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, ati Jeremoti, ati Sabadi, ati Asisa.

28. Ninu awọn ọmọ Bebai pẹlu; Jehohanani, Hananiah, Sabbai ati Atlai.

29. Ati ninu awọn ọmọ Bani; Meṣullamu, Malluki, ati Adaiah, Jaṣubu, ati Ṣeali ati Ramoti.

30. Ati ninu awọn ọmọ Pahat-moabu Adma ati Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleeli, ati Binnui, ati Manasse.

31. Ati ninu awọn ọmọ Harimu; Elieseri, Isṣjah, Malkiah, Ṣemaiah, Ṣimeoni,

32. Benjamini, Malluki, ati Ṣemariah.

33. Ninu awọn ọmọ Haṣumu; Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifeleti, Jeremai, Manasse, ati Ṣimei.

34. Ninu awọn ọmọ Bani; Maadai, Amramu ati Ueli.

35. Benaiah, Bedeiah, Kellu,

36. Faniah, Meremoti, Eliaṣibu,

37. Mattaniah, Mattenai ati Jaasau,

38. Ati Bani, ati Binnui, Ṣimei.

39. Ati Ṣelemiah, ati Natani, ati Adaiah,

40. Maknadebai, Saṣai, Ṣarai,

41. Asareeli, ati Ṣelemiah, Ṣemariah.

42. Ṣallumu, Amariah, ati Josefu.

43. Ninu awọn ọmọ Nebo; Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Ṣebina, Jadau, ati Joeli, Benaiah.

44. Gbogbo awọn yi li o mu ajeji obinrin ba wọn gbe, omiran ninu wọn si ni obinrin nipa ẹniti nwọn li ọmọ.